a
If 12.9
;
20.2
.
Genesis 3:1
Ìṣubú ènìyàn
1
a
Ejò sá à ṣe alárékérekè ju àwọn ẹranko igbó yòókù tí
Olúwa
Ọlọ́run dá lọ. Ó sọ fún obìnrin náà pé, “Ǹjẹ́ òtítọ́ ha ni Ọlọ́run wí pé, ‘Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ jẹ èso èyíkéyìí lára àwọn igi tí ó wà nínú ọgbà’?”
Copyright information for
YorBMYO